-
Sáàmù 95:11Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
11 Torí náà, mo búra nínú ìbínú mi pé:
“Wọn ò ní wọnú ìsinmi mi.”+
-
-
Hébérù 3:18Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
18 Àwọn wo ló sì búra fún pé wọn ò ní wọnú ìsinmi òun? Ṣebí àwọn tó ṣàìgbọràn ni?
-