-
Nọ́ńbà 22:16, 17Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
16 Wọ́n wá sọ́dọ̀ Báláámù, wọ́n sì sọ fún un pé: “Ohun tí Bálákì ọmọ Sípórì sọ nìyí, ‘Jọ̀ọ́, má ṣe jẹ́ kí ohunkóhun dí ọ lọ́wọ́ láti wá sọ́dọ̀ mi, 17 torí màá dá ọ lọ́lá gan-an, ohunkóhun tí o bá sì ní kí n ṣe ni màá ṣe. Torí náà, jọ̀ọ́ máa bọ̀, wá bá mi gégùn-ún fún àwọn èèyàn yìí.’”
-