-
1 Sámúẹ́lì 21:5Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
5 Dáfídì dá àlùfáà náà lóhùn pé: “A ti rí i dájú pé a yẹra fún àwọn obìnrin bí a ti máa ń ṣe nígbà tí mo bá jáde ogun.+ Tí ara àwọn ọkùnrin náà bá wà ní mímọ́ nígbà tó jẹ́ pé iṣẹ́ tí kò fi bẹ́ẹ̀ ṣe pàtàkì ni wọ́n bá lọ, ṣé wọn ò ní wà ní mímọ́ nígbà tí wọ́n fẹ́ ṣiṣẹ́ pàtàkì bíi tòní yìí?”
-