-
2 Sámúẹ́lì 23:24-39Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
24 Ásáhélì+ arákùnrin Jóábù wà lára àwọn ọgbọ̀n (30) náà, àwọn ni: Élíhánánì ọmọ Dódò ará Bẹ́tílẹ́hẹ́mù,+ 25 Ṣámà ará Háródù, Élíkà ará Háródù, 26 Hélésì+ tó jẹ́ Pálútì, Írà+ ọmọ Íkéṣì ará Tékóà, 27 Abi-ésérì+ ọmọ Ánátótì,+ Mébúnáì ọmọ Húṣà, 28 Sálímónì ọmọ Áhóhì, Máháráì+ ará Nétófà, 29 Hélébù ọmọ Báánà ará Nétófà, Ítáì ọmọ Ríbáì ará Gíbíà ti àwọn ọmọ Bẹ́ńjámínì, 30 Bẹnáyà+ ará Pírátónì, Hídáì tó wá láti àwọn àfonífojì Gááṣì,+ 31 Abi-álíbónì tó jẹ́ Ábátì, Ásímáfẹ́tì ará Báhúmù, 32 Élíábà tó jẹ́ Ṣáálíbónì, àwọn ọmọ Jáṣénì, Jónátánì, 33 Ṣámà tó jẹ́ Hárárì, Áhíámù ọmọ Ṣárárì tó jẹ́ Hárárì, 34 Élífélétì ọmọ Áhásíbáì ọmọ ará Máákátì, Élíámù ọmọ Áhítófẹ́lì+ ará Gílò, 35 Hésírò ará Kámẹ́lì, Pááráì ará Árábù, 36 Ígálì ọmọ Nátánì ará Sóbà, Bánì ọmọ Gádì, 37 Sélékì ọmọ Ámónì, Náháráì ará Béérótì, tó ń bá Jóábù ọmọ Seruáyà gbé ìhámọ́ra, 38 Írà tó jẹ́ Ítírì, Gárébù tó jẹ́ Ítírì,+ 39 Ùráyà+ ọmọ Hétì, gbogbo wọn jẹ́ mẹ́tàdínlógójì (37).
-