2 Àwọn Ọba 24:8, 9 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 8 Ọmọ ọdún méjìdínlógún (18) ni Jèhóákínì+ nígbà tó jọba, oṣù mẹ́ta ló sì fi ṣàkóso ní Jerúsálẹ́mù.+ Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Néhúṣítà ọmọ Élínátánì láti Jerúsálẹ́mù. 9 Ó ń ṣe ohun tó burú ní ojú Jèhófà, gbogbo ohun tí bàbá rẹ̀ ṣe ni òun náà ṣe.
8 Ọmọ ọdún méjìdínlógún (18) ni Jèhóákínì+ nígbà tó jọba, oṣù mẹ́ta ló sì fi ṣàkóso ní Jerúsálẹ́mù.+ Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Néhúṣítà ọmọ Élínátánì láti Jerúsálẹ́mù. 9 Ó ń ṣe ohun tó burú ní ojú Jèhófà, gbogbo ohun tí bàbá rẹ̀ ṣe ni òun náà ṣe.