Máàkù 16:1 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 16 Torí náà, nígbà tí Sábáàtì+ ti kọjá, Màríà Magidalénì, Màríà+ ìyá Jémíìsì àti Sàlómẹ̀ ra àwọn èròjà tó ń ta sánsán kí wọ́n lè wá fi pa á lára.+ Lúùkù 23:55, 56 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 55 Àmọ́ àwọn obìnrin tó bá a wá láti Gálílì tẹ̀ lé e lọ, wọ́n yọjú wo ibojì* náà, wọ́n sì rí i bí wọ́n ṣe tẹ́ òkú rẹ̀,+ 56 wọ́n wá pa dà lọ pèsè èròjà tó ń ta sánsán àti àwọn òróró onílọ́fínńdà. Àmọ́ wọ́n sinmi ní Sábáàtì+ bí a ṣe pa á láṣẹ. Jòhánù 19:40 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 40 Torí náà, wọ́n gbé òkú Jésù, wọ́n sì fi aṣọ ọ̀gbọ̀* dì í pẹ̀lú àwọn èròjà tó ń ta sánsán náà,+ bí àwọn Júù ṣe máa ń sìnkú.
16 Torí náà, nígbà tí Sábáàtì+ ti kọjá, Màríà Magidalénì, Màríà+ ìyá Jémíìsì àti Sàlómẹ̀ ra àwọn èròjà tó ń ta sánsán kí wọ́n lè wá fi pa á lára.+
55 Àmọ́ àwọn obìnrin tó bá a wá láti Gálílì tẹ̀ lé e lọ, wọ́n yọjú wo ibojì* náà, wọ́n sì rí i bí wọ́n ṣe tẹ́ òkú rẹ̀,+ 56 wọ́n wá pa dà lọ pèsè èròjà tó ń ta sánsán àti àwọn òróró onílọ́fínńdà. Àmọ́ wọ́n sinmi ní Sábáàtì+ bí a ṣe pa á láṣẹ.
40 Torí náà, wọ́n gbé òkú Jésù, wọ́n sì fi aṣọ ọ̀gbọ̀* dì í pẹ̀lú àwọn èròjà tó ń ta sánsán náà,+ bí àwọn Júù ṣe máa ń sìnkú.