ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Nọ́ńbà 14:19, 20
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 19 Jọ̀ọ́, ro ti ìfẹ́ rẹ tí kì í yẹ̀ tó pọ̀ gan-an, kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn èèyàn yìí jì wọ́n, bí o ṣe ń dárí jì wọ́n láti Íjíbítì títí di báyìí.”+

      20 Jèhófà wá sọ pé: “Mo dárí jì wọ́n bí o ṣe sọ.+

  • Jeremáyà 30:11
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 11 “Nítorí mo wà pẹ̀lú rẹ,” ni Jèhófà wí, “láti gbà ọ́.

      Ṣùgbọ́n màá pa gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí mo tú ọ ká sí àárín wọn run;+

      Àmọ́ ní tìrẹ, mi ò ní pa ọ́ run.+

      Mi ò ní bá ọ wí* kọjá ààlà,

      Mi ò sì ní ṣàìfi ìyà jẹ ọ́.”+

  • Ìdárò 3:22
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 22 Nítorí ìfẹ́ Jèhófà tí kì í yẹ̀ ni ò jẹ́ ká ṣègbé,+

      Nítorí àánú rẹ̀ kò ní dópin láé.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́