ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Àwọn Onídàájọ́ 4:2
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 2 Torí náà, Jèhófà fi wọ́n lé ọwọ́ Jábínì ọba Kénáánì,+ tó jọba ní Hásórì. Sísérà ni olórí àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ó sì ń gbé ní Háróṣétì+ ti àwọn orílẹ̀-èdè.*

  • Àwọn Onídàájọ́ 4:7
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 7 Màá mú Sísérà, olórí àwọn ọmọ ogun Jábínì wá bá ọ, tòun ti àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ wá sí odò* Kíṣónì,+ màá sì fi lé ọ lọ́wọ́.’”+

  • Àwọn Onídàájọ́ 4:15
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 15 Jèhófà wá mú kí nǹkan dà rú mọ́ Sísérà lójú+ pẹ̀lú gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun àti gbogbo ọmọ ogun rẹ̀ níwájú idà Bárákì. Nígbà tó yá, Sísérà sọ̀ kalẹ̀ nínú kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó sì sá lọ.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́