2 Torí náà, Jèhófà fi wọ́n lé ọwọ́ Jábínì ọba Kénáánì,+ tó jọba ní Hásórì. Sísérà ni olórí àwọn ọmọ ogun rẹ̀, ó sì ń gbé ní Háróṣétì+ ti àwọn orílẹ̀-èdè.*
15 Jèhófà wá mú kí nǹkan dà rú mọ́ Sísérà lójú+ pẹ̀lú gbogbo kẹ̀kẹ́ ogun àti gbogbo ọmọ ogun rẹ̀ níwájú idà Bárákì. Nígbà tó yá, Sísérà sọ̀ kalẹ̀ nínú kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀, ó sì sá lọ.