10 Nítorí mo ti gbọ́ ọ̀pọ̀ àhesọ ọ̀rọ̀ tó burú;
Ohun ẹ̀rù yí mi ká.+
“Ẹ fẹ̀sùn kàn án; ẹ jẹ́ ká fẹ̀sùn kàn án!”
Gbogbo àwọn tó ń sọ pé àwọn fẹ́ àlàáfíà fún mi, ìṣubú mi ni wọ́n ń wá:+
“Bóyá ó máa ṣàṣìṣe torí pé kò kíyè sára,
Tí a ó sì lè borí rẹ̀, kí a sì gbẹ̀san lára rẹ̀.”