-
Nọ́ńbà 21:28Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
28 Torí iná jáde wá láti Hẹ́ṣíbónì, ọwọ́ iná láti ìlú Síhónì.
Ó ti jó Árì ti Móábù run, àwọn olúwa àwọn ibi gíga Áánónì.
-
-
Diutarónómì 2:9Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
9 Jèhófà wá sọ fún mi pé, ‘Má ṣe bá Móábù fa wàhálà kankan, má sì bá wọn jagun, torí mi ò ní fún ọ ní ìkankan lára ilẹ̀ rẹ̀ pé kó di tìrẹ, torí mo ti fún àwọn àtọmọdọ́mọ Lọ́ọ̀tì ní Árì kó lè di tiwọn.+
-