-
Jeremáyà 4:11Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
11 Nígbà yẹn, a ó sọ fún àwọn èèyàn yìí àti Jerúsálẹ́mù pé:
“Ẹ̀fúùfù gbígbóná láti orí àwọn òkè tó wà ní aṣálẹ̀ tí kò sí ohunkóhun tó hù lórí wọn
Ló máa gbá ọmọbìnrin* àwọn èèyàn mi lọ;
Kì í ṣe pé ó máa wá fẹ́ ọkà tàbí pàǹtírí.
-
-
Ìsíkíẹ́lì 13:13Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
13 “Torí náà, ohun tí Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ sọ nìyí, ‘Màá fi ìbínú mú kí ìjì líle jà, màá fi ìrunú rọ àrọ̀ọ̀rọ̀dá òjò, ìbínú tó le ni màá sì fi rọ yìnyín láti pa á run.
-