-
Jóṣúà 24:20Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
20 Tí ẹ bá fi Jèhófà sílẹ̀, tí ẹ sì ń sin àwọn ọlọ́run àjèjì, òun náà máa kẹ̀yìn sí yín, ó sì máa pa yín run lẹ́yìn tó ti ṣe ohun rere fún yín.”+
-
-
2 Kíróníkà 7:19, 20Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
19 Àmọ́ tí ẹ bá pa dà lẹ́yìn mi, tí ẹ kò sì pa àwọn òfin àti àṣẹ tí mo fún yín mọ́, tí ẹ wá lọ ń sin àwọn ọlọ́run míì, tí ẹ sì ń forí balẹ̀ fún wọn,+ 20 ńṣe ni màá fa Ísírẹ́lì tu lórí ilẹ̀ mi tí mo fún wọn,+ màá gbé ilé yìí tí mo yà sí mímọ́ fún orúkọ mi sọ nù kúrò níwájú mi, màá sọ ọ́ di ohun ẹ̀gàn* àti ohun ẹ̀sín láàárín gbogbo èèyàn.+
-