-
Jeremáyà 5:12, 13Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
Àjálù kankan kò ní bá wa;
A kò ní rí idà tàbí ìyàn.’+
13 Àwọn wòlíì jẹ́ àgbá òfìfo,
Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run kò sì sí lẹ́nu wọn.
Kí ó rí bẹ́ẹ̀ fún wọn!”
-
-
Jeremáyà 23:15Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
15 Nítorí náà, ohun tí Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun sọ sí àwọn wòlíì náà nìyí:
Nítorí láti ọ̀dọ̀ àwọn wòlíì Jerúsálẹ́mù ni ìpẹ̀yìndà ti tàn káàkiri ilẹ̀ náà.”
-
-
Ìsíkíẹ́lì 12:24Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
24 Torí kò ní sí ìran èké tàbí ìwoṣẹ́ ẹ̀tàn mọ́ nínú ilé Ísírẹ́lì.+
-