-
Ẹ́kísódù 20:2Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
2 “Èmi ni Jèhófà Ọlọ́run rẹ, ẹni tó mú ọ kúrò ní ilẹ̀ Íjíbítì, kúrò ní ilé ẹrú.+
-
-
Jeremáyà 23:7, 8Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
7 “Síbẹ̀, ìgbà kan ń bọ̀,” ni Jèhófà wí, “tí wọn ò ní máa sọ pé: ‘Bí Jèhófà ti wà láàyè, ẹni tó mú àwọn èèyàn Ísírẹ́lì jáde kúrò ní ilẹ̀ Íjíbítì!’+ 8 kàkà bẹ́ẹ̀, wọ́n á máa sọ pé: ‘Bí Jèhófà ti wà láàyè, ẹni tó mú àwọn ọmọ ilé Ísírẹ́lì jáde kúrò, tó sì mú wọn wọlé wá láti ilẹ̀ àríwá àti gbogbo ilẹ̀ tó tú wọn ká sí!’ wọ́n á sì máa gbé lórí ilẹ̀ tiwọn.”+
-