-
Ìsíkíẹ́lì 36:5Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
5 ohun tí Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ sọ fún àwọn yìí ni pé: ‘Èmi yóò fi ìtara mi tó ń jó bí iná+ sọ̀rọ̀ sí àwọn tó là á já nínú àwọn orílẹ̀-èdè àti sí gbogbo Édómù, àwọn tí inú wọn dùn gan-an, tí wọ́n sì fi mí ṣẹlẹ́yà*+ nígbà tí wọ́n sọ ilẹ̀ mi di ohun ìní wọn, kí wọ́n lè gba àwọn ibi ìjẹko inú ilẹ̀ náà, kí wọ́n sì kó ohun tó wà nínú rẹ̀.’”’+
-