ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Máàkù 14:62
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 62 Jésù wá sọ pé: “Èmi ni; ẹ sì máa rí Ọmọ èèyàn+ tó jókòó ní ọwọ́ ọ̀tún agbára,+ tó sì ń bọ̀ pẹ̀lú àwọsánmà* ojú ọ̀run.”+

  • Jòhánù 5:18
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 18 Ìdí nìyí tí àwọn Júù fi túbọ̀ ń wá bí wọ́n ṣe máa pa á, torí kì í ṣe pé kò pa Sábáàtì mọ́ nìkan ni, àmọ́ ó tún ń pe Ọlọ́run ní Baba rẹ̀,+ ó ń sọ pé òun àti Ọlọ́run dọ́gba.+

  • Jòhánù 10:36
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 36 ṣé èmi tí Baba sọ di mímọ́, tó sì rán wá sí ayé lẹ wá ń sọ fún pé, ‘O sọ̀rọ̀ òdì,’ torí mo sọ pé, ‘Ọmọ Ọlọ́run ni mí’?+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́