ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Mátíù 9:10, 11
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 10 Lẹ́yìn náà, bó ṣe ń jẹun* nínú ilé, wò ó! ọ̀pọ̀ àwọn agbowó orí àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ wá, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí í bá Jésù àti àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ jẹun.*+ 11 Àmọ́ nígbà tí àwọn Farisí rí èyí, wọ́n sọ fún àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ pé: “Kí ló dé tí olùkọ́ yín ń bá àwọn agbowó orí àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹun?”+

  • Máàkù 2:15, 16
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 15 Lẹ́yìn náà, nígbà tó ń jẹun* nílé rẹ̀, ọ̀pọ̀ àwọn agbowó orí àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ń bá Jésù àti àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ jẹun,* torí pé ọ̀pọ̀ nínú wọn ló ń tẹ̀ lé e.+ 16 Àmọ́ nígbà tí àwọn akọ̀wé òfin lára àwọn Farisí rí i pé ó ń bá àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ àti àwọn agbowó orí jẹun, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í sọ fún àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀ pé: “Ṣé ó máa ń bá àwọn agbowó orí àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹun ni?”

  • Lúùkù 5:29, 30
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 29 Léfì wá gbà á lálejò, ó se àsè rẹpẹtẹ fún un nílé rẹ̀, àwọn agbowó orí àti àwọn míì tó ń bá wọn jẹun* sì pọ̀ gan-an níbẹ̀.+ 30 Ni àwọn Farisí àti àwọn tó jẹ́ akọ̀wé òfin lára wọn bá bẹ̀rẹ̀ sí í kùn sí àwọn ọmọ ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n ń sọ pé: “Kí ló dé tí ẹ̀ ń bá àwọn agbowó orí àti àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ jẹun, tí ẹ sì ń bá wọn mu?”+

  • 1 Tímótì 1:15
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 15 Ọ̀rọ̀ yìí ṣeé gbára lé, ó sì yẹ ká gbà á délẹ̀délẹ̀, pé: Kristi Jésù wá sí ayé láti gba àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ là.+ Èmi sì ni ẹni àkọ́kọ́ lára wọn.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́