ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Ìṣe 23:6
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 6 Nígbà tí Pọ́ọ̀lù rí i pé apá kan wọn jẹ́ Sadusí, àwọn tó kù sì jẹ́ Farisí, ó ké jáde ní Sàhẹ́ndìrìn pé: “Ẹ̀yin èèyàn, ẹ̀yin ará, Farisí ni mí,+ mo sì jẹ́ ọmọ àwọn Farisí. Torí ìrètí àjíǹde àwọn òkú ni wọ́n ṣe ń dá mi lẹ́jọ́.”

  • Ìṣe 26:4, 5
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 4 “Ní tòótọ́, irú ìgbésí ayé tí mo gbé láti ìgbà èwe mi láàárín àwọn èèyàn* mi àti ní Jerúsálẹ́mù ni gbogbo àwọn Júù mọ̀ dáadáa,+ 5 ìyẹn àwọn tó ti mọ̀ mí tipẹ́tipẹ́, tí wọ́n bá fẹ́, wọ́n lè jẹ́rìí sí i pé ìgbé ayé Farisí ni mo gbé+ ní ìlànà ẹ̀ya ìsìn tí kò gba gbẹ̀rẹ́ rárá,+ ti ọ̀nà ìjọsìn wa.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́