ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Ìsíkíẹ́lì 15
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ìsíkíẹ́lì

      • Àjàrà tí kò wúlò ni Jerúsálẹ́mù (1-8)

Ìsíkíẹ́lì 15:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 80:14-16; Ais 5:24; Jer 7:20; Isk 20:47

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Àwọn Ìtẹ̀jáde Tá A Tọ́ka sí Nínú Ìwé Ìpàdé,

    7/2017, ojú ìwé 2

Ìsíkíẹ́lì 15:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Isk 6:7; 7:4

Ìsíkíẹ́lì 15:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 6:11; Jer 25:11; Isk 6:14
  • +2Kr 36:14

Àwọn míì

Ìsík. 15:6Sm 80:14-16; Ais 5:24; Jer 7:20; Isk 20:47
Ìsík. 15:7Isk 6:7; 7:4
Ìsík. 15:8Ais 6:11; Jer 25:11; Isk 6:14
Ìsík. 15:82Kr 36:14
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ìsíkíẹ́lì 15:1-8

Ìsíkíẹ́lì

15 Jèhófà tún bá mi sọ̀rọ̀, ó ní: 2 “Ọmọ èèyàn, ọ̀nà wo ni igi àjàrà gbà jọ àwọn igi yòókù tàbí àwọn ẹ̀ka igi inú igbó? 3 Ǹjẹ́ igi rẹ̀ wúlò fún iṣẹ́ kankan? Àbí àwọn èèyàn lè fi igi rẹ̀ ṣe èèkàn tí wọ́n á máa fi nǹkan kọ́? 4 Wò ó! Wọ́n fi dáná, iná jó o lórí àti ní ìdí, àárín rẹ̀ sì gbẹ. Ṣé ó wá wúlò fún iṣẹ́ kankan báyìí? 5 Nígbà tó ṣì wà lódindi, kò wúlò fún ohunkóhun. Ká má ṣẹ̀ṣẹ̀ wá sọ ìgbà tí iná jó o, tó sì gbẹ!”

6 “Torí náà, ohun tí Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ sọ nìyí: ‘Bí igi àjàrà láàárín àwọn igi inú igbó, tí mo ti sọ di ohun ìdáná, bẹ́ẹ̀ ni màá ṣe fún àwọn tó ń gbé Jerúsálẹ́mù.+ 7 Mo ti gbéjà kò wọ́n. Wọ́n bọ́ lọ́wọ́ iná, síbẹ̀ iná máa jó wọn run. Ẹ ó sì wá mọ̀ pé èmi ni Jèhófà, nígbà tí mo bá gbéjà kò wọ́n.’”+

8 “‘Èmi yóò sì sọ ilẹ̀ náà di ahoro,+ torí pé wọ́n ti hùwà àìṣòótọ́,’+ ni Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ wí.”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́