ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w13 12/15 ojú ìwé 32
  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2013

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2013
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
w13 12/15 ojú ìwé 32

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2013

Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

  • A Ti Sọ Yín Di Mímọ́, 8/15

  • Àwọn Alàgbà Jẹ́ ‘Alábàáṣiṣẹ́pọ̀ fún Ìdùnnú Wa,’ 1/15

  • Àwọn Ìránnilétí Jèhófà Ṣeé Gbẹ́kẹ̀ Lé, 9/15

  • Báwo La Ṣe Lè Máa Ní “Ẹ̀mí Ìdúródeni”? 11/15

  • Dúró sí Ibi Ààbò Jèhófà, 2/15

  • Èyí Ni Ogún Tẹ̀mí Wa, 2/15

  • ‘Èyí Yóò sì Jẹ́ Ìrántí fún Yín,’ 12/15

  • Ẹ̀kọ́ Tó Wà Nínú Àdúrà Tí Wọ́n Ronú Jinlẹ̀ Gbà, 10/15

  • Ẹ Má Ṣe Jẹ́ Kí Àárẹ̀ Mú Yín, 4/15

  • Ẹ Má Ṣe “Tètè Mì Kúrò Nínú Ìmọnúúrò Yín”! 12/15

  • Ẹ Máa Bá Ara Yín Sọ̀rọ̀ Kẹ́ Ẹ Lè Túbọ̀ Ṣera Yín Lọ́kan, 5/15

  • Ẹ Máa Gba Ti Ara Yín Rò Kẹ́ Ẹ sì Máa fún Ara Yín Ní Ìṣírí, 8/15

  • “Ẹ Máa Sìnrú fún Jèhófà,” 10/15

  • “Ẹ Máa Ṣe Èyí ní Ìrántí Mi,” 12/15

  • Ẹ Máa Wádìí Dájú Àwọn Ohun Tí Ó Ṣe Pàtàkì Jù, 4/15

  • ‘Ẹ Wà Lójúfò Kí Ẹ Lè Máa Gbàdúrà,” 11/15

  • Ẹ̀yin Òbí Àtẹ̀yin Ọmọ, Ẹ Máa Fìfẹ́ Bá Ara Yín Sọ̀rọ̀, 5/15

  • Ẹ̀yin Olùṣọ́ Àgùntàn, Ẹ Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Àwọn Olùṣọ́ Àgùntàn Ńlá Náà, 11/15

  • Fi Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run Ran Ara Rẹ àti Àwọn Míì Lọ́wọ́, 4/15

  • Iṣẹ́ Aṣáájú-Ọ̀nà Máa Jẹ́ Kó O Túbọ̀ Sún Mọ́ Ọlọ́run, 9/15

  • Ìṣẹ̀dá Ń Jẹ́ Ká Mọ̀ Nípa Ọlọ́run Alààyè, 10/15

  • Jàǹfààní Kíkún Látinú Kíka Bíbélì Déédéé, 4/15

  • Jèhófà Ni Ibùgbé Wa, 3/15

  • Jésù Ń Tipasẹ̀ Àwọn Èèyàn Kéréje Bọ́ Ọ̀pọ̀ Èèyàn, 7/15

  • Jẹ́ Adúróṣinṣin Kó O sì Máa Dárí Jini Bíi Ti Jèhófà, 6/15

  • Jẹ́ Kí Amọ̀kòkò Tí Kò Lẹ́gbẹ́ Náà Mọ Ẹ́, 6/15

  • Jẹ́ Kí Àwọn Ìránnilétí Jèhófà Máa Múnú Rẹ Dùn, 9/15

  • Jẹ́ Onígboyà, Jèhófà Wà Pẹ̀lú Rẹ! 1/15

  • Jẹ́ Ọ̀làwọ́ Kó O sì Máa Fòye Báni Lò Bíi Ti Jèhófà, 6/15

  • ‘Kò Sí Ohun Ìkọ̀sẹ̀’ fún Àwọn Tó Nífẹ̀ẹ́ Jèhófà, 3/15

  • Má Ṣe Jẹ́ Kí Ohunkóhun Mú Ẹ Jìnnà sí Jèhófà, 1/15

  • Má Ṣe “Kún fún Ìhónú sí Jèhófà,” 8/15

  • Máa Fi Ọgbọ́n Ṣe Ìpinnu, 9/15

  • Máa Gbé Orúkọ Ńlá Jèhófà Ga, 3/15

  • Máa Ronú Nípa Irú Ẹni Tó Yẹ Kó O Jẹ́, 8/15

  • Máa Ṣe Ìpinnu Tó Dára Kó O Má Bàa Pàdánù Ogún Tẹ̀mí Rẹ, 5/15

  • Máa Ṣe Ohun Tí Jésù Sọ Nínú Àdúrà Onífẹ̀ẹ́ Tó Gbà, 10/15

  • Máa Ṣe Ojúṣe Rẹ Gẹ́gẹ́ Bí Ajíhìnrere, 5/15

  • Ní Báyìí Tá A Ti “Wá Mọ Ọlọ́run”—Kí Ló Kàn? 3/15

  • “Ní Ti Tòótọ́, Ta Ni Ẹrú Olóòótọ́ àti Olóye?” 7/15

  • Ǹjẹ́ Ẹ Ti Para Dà? 9/15

  • Ǹjẹ́ O Mọyì Ogún Tẹ̀mí Wa? 2/15

  • Ǹjẹ́ O Ní Ìtara fún “Iṣẹ́ Àtàtà”? 5/15

  • Ǹjẹ́ Ó Wù Ẹ́ Láti Mọ Jèhófà? 3/15

  • O Lè Sin Jèhófà Kó O Má sì Kábàámọ̀, 1/15

  • Olùṣọ́ Àgùntàn Méje àti Mọ́gàjí Mẹ́jọ Ti Òde Òní, 11/15

  • Sá fún Àwọn Nǹkan Tí Kò Ní Jẹ́ Kí Ọlọ́run Dá Ẹ Lọ́lá, 2/15

  • Sọ fún Wa, Ìgbà Wo Ni Nǹkan Wọ̀nyí Yóò Ṣẹlẹ̀? 7/15

  • Ṣègbọràn sí Àwọn Olùṣọ́ Àgùntàn Tí Jèhófà Yàn, 11/15

  • Ṣé Wàá Yááfì Àwọn Nǹkan Torí Ìjọba Ọlọ́run? 12/15

  • Túbọ̀ Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Nípa Àwọn Ànímọ́ Jèhófà, 6/15

  • Túbọ̀ Sún Mọ́ Jèhófà, 1/15

  • “Wò ó! Mo Wà Pẹ̀lú Yín ní Gbogbo Àwọn Ọjọ́,” 7/15

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

  • “Àwòrán Yìí Mà Dára Gan-an O!” 7/15

  • Àwọn Àpéjọ Àgbègbè ‘Òtítọ́ Ni Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run!’ 5/1

  • Ẹnì Kan Ṣẹ̀ṣẹ̀ Di Ara Ìgbìmọ̀ Olùdarí (M. Sanderson), 7/15

  • Inú Ọba Dùn! (Swaziland), 8/15

  • Jèhófà Dáàbò Bò Wọ́n (lábẹ́ Ìjọba Násì), 12/15

  • “Mánigbàgbé” (Àwòkẹ́kọ̀ọ́ Nípa Ìṣẹ̀dá), 2/15

  • Má Ṣe Sọ̀rètí Nù! 3/15

  • “Mò Ń Gbé Ilé Mi Kiri bí Ìgbín” (ọkọ̀ àfiṣelé), 11/15

  • Ọmọbìnrin Kan Lo Ìdánúṣe (Chile), 1/15

  • Sí Òǹkàwé Wa (Ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́), 1/1

  • Sísin Ọlọ́run Ni Oògùn Àìsàn Rẹ̀! 11/15

  • Wọ́n Dúró Ṣinṣin ní “Wákàtí Ìdánwò” (Ogun Àgbáyé Kìíní), 5/15

  • Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn ní Mẹ́síkò, 4/15

  • Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn ní Norway, 1/15

  • Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn ní Philippines, 10/15

BÍBÉLÌ

  • Ìṣura Tó Fara Sin Láti Ọgọ́rọ̀ọ̀rún Ọdún (Bíbélì lédè Georgian), 6/1

  • Kí Ló Wà Nínú Bíbélì? 10/1

  • Ṣeé Lóye, 4/1

BÍBÉLÌ MÁA Ń YÍ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀWỌN ÈÈYÀN PA DÀ

  • “Èmi Fúnra Mi Wádìí Láti Mọ Ohun Tí Bíbélì Sọ” (L. Alifonso), 2/1

  • “Ìwà Mi Burú Jáì” (E. Leinonen), 4/1

  • “Kò Ṣe Mí Mọ́ Bíi Pé Mo Gbọ́dọ̀ Yí Ayé Yìí Pa Dà” (J. Sylgren), 7/1

  • ‘Mo Ronú Gidigidi Nípa Ibi Tí Mo Ń Bọ́rọ̀ Ayé Mi Lọ’ (A. Hancock), 8/1

  • ‘Nígbẹ̀yìngbẹ́yín Mo Ní Ojúlówó Òmìnira’ (B. Hewitt), 1/1

  • “Ó Wù Mí Kí N Di Àlùfáà” (R. Pacheco), 5/1

  • ‘Ọ̀pọ̀ Èèyàn Kórìíra Mi’ (W. Moya), 10/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

  • Àwọn wo ni “àwọn ọmọ Ọlọ́run tòótọ́”? (Jẹ 6:2, 4), 6/15

  • Kí ló fà á tí Jésù fi da omijé lójú? (Jo 11:35), 9/15

  • Ní Ísírẹ́lì ìgbàanì, ṣé wọ́n máa ń kan àwọn ọ̀daràn tí wọ́n bá fẹ́ pa mọ́ igi? 5/15

  • Ǹjẹ́ ó yẹ kí àwọn òbí máa jókòó ti ọmọ wọn tá a yọ lẹ́gbẹ́ láwọn ìpàdé ìjọ? 8/15

  • Ó “Wàásù fún Àwọn Ẹ̀mí Nínú Ẹ̀wọ̀n” (1Pe 3:19), 6/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

  • Àwọn Tó Tún Ìgbéyàwó Ṣe, 7/1

  • Bá Ọmọ Sọ̀rọ̀ Láìsí Àríyànjiyàn, 11/1

  • Bí Àárín Àwọn Tó Tún Ìgbéyàwó Ṣe àti Àwọn Ẹlòmíì Ṣe Lè Tòrò, 5/1

  • Ẹ̀yin Alàgbà, Ẹ Máa Tu “Ọkàn Tí Àárẹ̀ Mú” Lára? 6/15

  • Ẹ̀yin Òbí, Ẹ Kọ́ Ọmọ Yín Láti Kékeré, 8/15

  • Gba Ìtùnú, Kó O sì Tu Àwọn Míì Nínú, 3/15

  • Ikú Ọkọ Tàbí Aya, 12/15

  • Kí La Rí Kọ́ Nínú Ohun Tó Ṣẹlẹ̀ sí Ọ̀daràn Kan? 6/1

  • Lẹ́yìn Ìkọ̀sílẹ̀, 10/1

  • Má Ṣe Jẹ́ Kí Ọkàn Rẹ Tàn Ẹ́ Jẹ, 2/15

  • Pétérù Parọ́, Ananíà Náà Parọ́—Ẹ̀kọ́ Wo Ni Èyí Kọ́ Wa? 3/1

  • Ṣé Wàá Túbọ̀ Máa Kìlọ̀ Fáwọn Èèyàn? 10/15

  • Tí Ọmọ Bá Jẹ́ Abirùn, 2/1

  • Tọkọtaya Lè Láyọ̀ Kí Wọ́n sì Máa Bá Ara Wọn Gbé Títí Lọ, 9/1

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

  • A Fi Àádọ́ta Ọdún Ṣe Iṣẹ́ Ìsìn ní Ilẹ̀ Olótùútù (A. àti A. Mattila), 4/15

  • A Ṣe Tán Láti Sin Jèhófà Níbikíbi Tó Bá Fẹ́ (M. àti J. Hartlief), 7/15

  • Ìgbẹ́kẹ̀lé Nínú Jèhófà Mú Èrè Wá (M. Allen), 10/15

  • Iṣẹ́ Jèhófà Ni Mo Fi Ìgbésí Ayé Mi Ṣe (B. Walden), 12/1

  • Jèhófà Bù Kún Mi Gan-an Torí Pé Mo Ṣègbọràn Sí I (E. Piccioli), 6/15

  • Jèhófà ‘Ń Bá Mi Gbé Ẹrù Mi Lójoojúmọ́’ (M. du Raan), 8/15

  • “Mo Rí I, Ṣùgbọ́n Kò Yé Mi” (O. Hamel), 3/1

  • Ohun Tó Mú Kí Ìgbésí Ayé Wa Nítumọ̀ (P. Smith), 5/15

  • Tálákà Ni Wá àmọ́ À Ń Fi Ayọ̀ Sin Ọlọ́run (A. Ursu), 9/1

JÈHÓFÀ

  • ‘Àwọn Ànímọ́ Rẹ̀ Tí A Kò Lè Rí Ṣe Kedere,’ 8/1

  • Àwọn Irọ́ Tí Kò Jẹ́ Káwọn Èèyàn Nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́run, 11/1

  • ‘Èwo Ni Èkínní Nínú Òfin?’ 3/1

  • “Ẹ Máa Bá A Nìṣó Ní Bíbéèrè,” 4/1

  • “Jèhófà Dárí Jì Yín,” 10/1

  • Jèhófà “Kì Í Ṣe Ojúsàájú,” 6/1

  • Ǹjẹ́ A Nílò Ọlọ́run? 12/1

  • Ǹjẹ́ Ìyà Tó Ń Jẹ Wá Kan Ọlọ́run? 7/1

  • Ǹjẹ́ Ọ̀rọ̀ Rẹ Jẹ Jèhófà Lógún Lóòótọ́? 5/1

  • “Ń Sọ Ohun Gbogbo Di Tuntun,” 12/1

  • Ohun Tí O Bá Ṣe Lè Dun Ọlọ́run, 9/1

  • ‘Olùsẹ̀san fún Àwọn Tí Ń Wá A,’ 11/1

  • Ó ‘Ń Mú Inú Wa Dùn,’ 7/1

  • Orúkọ, 1/1

  • ‘O Ti Ṣí Wọn Payá fún Àwọn Ìkókó,’ 1/1

  • ‘Ọlọ́run Àwọn Alààyè,’ 2/1

  • “Ọlọ́run Nífẹ̀ẹ́ Olùfúnni Ọlọ́yàyà,” 9/1

  • Ṣé Gbogbo Àdúrà ni Ọlọ́run Máa Ń Gbọ́? 8/1

  • Ṣé Ìkà Ni Ọlọ́run? 5/1

JÉSÙ KRISTI

  • Àjíǹde, 3/1

  • Báwo Ló Ṣe Yẹ Ká Máa Rántí Rẹ̀? 12/1

  • Ìgbà Wo Ni Ọlọ́run Dá A? 3/1

  • Ìpadàbọ̀ Kristi, 12/1

  • Ìsìnkú, 3/1

  • Kí Nìdí Tí Wọ́n Fi Ń Pè É Ní Ọmọ Ọlọ́run? 3/1

  • Ṣé Ọ̀run Ni Jésù Sọ Pé Aṣebi Yóò Lọ? 3/1

Ọ̀KAN-Ọ̀-JỌ̀KAN

  • Àfiwé Máa Ń Mú Kí Ọ̀rọ̀ Yéni, 9/15

  • Àjíǹde, 10/1

  • Àlááfíà Lórí Ilẹ̀ Ayé, 6/1

  • A ‘Polongo Rẹ̀ Ní Olódodo Nípa Àwọn Iṣẹ́’ (Ráhábù), 11/1

  • Àwòrán Oníhòòhò—Ó Léwu àbí Kò Léwu? 8/1

  • Àwọn Júù Máa Ń Ṣe Ìgbátí Yí Òrùlé Ilé Wọn Ká, 4/1

  • Àwọn Wo Ló Ń Lọ sí Ọ̀run? 11/1

  • Bá A Ṣe Lè Ṣèrànwọ́ fún Àwọn Èèyàn, 11/15

  • Bàbà (ohun tí wọ́n lò ó fún látijọ̀), 12/1

  • Bí Àwọn Júù Ọgọ́rùn-ún Ọdún Kìíní Ṣe Ń Múra Òkú Sílẹ̀ Kí Wọ́n Tó Sin Ín, 3/1

  • Bí Àwọ̀ Ṣe Ń Nípa Lórí Rẹ, 10/1

  • Èlíṣà Rí Kẹ̀kẹ́ Ẹṣin Oníná, 8/15

  • Ẹ̀ṣọ́ Olú Ọba Gbọ́ Ìhìn Rere, 2/15

  • Ẹ̀tanú—Ìṣòro Tó Kárí Ayé, 6/1

  • Ìbátan Káyáfà Ni, 2/15

  • Ibi Tí Èṣù Ti Wá, 2/1

  • Ìdí Tí Bíbélì Kò Fi Dárúkọ Àwọn Kan, 8/1

  • Ìgbésí Ayé Lè Ládùn, 4/1

  • Ìhìn Rere Júdásì, 2/1

  • Kí Nìdí Tí Ìyà Fi Pọ̀ Láyé? 9/1

  • Mósè, 2/1

  • Nínéfè “Ìlú Ńlá Ìtàjẹ̀sílẹ̀,” 4/1

  • Ǹjẹ́ Èèyàn Lè Wà Láàyè Títí Láé? 7/1

  • Ǹjẹ́ Ó Yẹ Ká Máa Gbàdúrà sí Àwọn Ẹni Mímọ́? 6/1

  • Ǹjẹ́ Ó Yẹ Kí O Gbára Lé Ẹ̀sìn? 7/1

  • Ǹjẹ́ Ọlọ́run Lè Dárí Ẹ̀ṣẹ̀ Jì? 5/1

  • Ǹjẹ́ Wọ́n Tún Tẹ́ńpìlì Jerúsálẹ́mù Kọ́ Lẹ́yìn Ọdún 70 Sànmánì Kristẹni? 4/15

  • Ó ‘Bá Ọlọ́run Rìn’ (Nóà), 4/1

  • “Ó Ń Sọ̀rọ̀ Síbẹ̀” (Ébẹ́lì), 1/1

  • Òpin Ayé, 1/1

  • Ọlọ́run Pa Nóà “Mọ́ Láìséwu Pẹ̀lú Àwọn Méje Mìíràn,” 8/1

  • Ṣé “Ilé Gogoro Bábélì” Ni Èdè Ti Bẹ̀rẹ̀? 9/1

  • Ṣé Josephus Ló Kọ Ọ́ Lóòótọ́? 3/15

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́