ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w23 November ojú ìwé 1-32
  • Ilé Ìṣọ́ Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ilé Ìṣọ́ Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2023
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2023
w23 November ojú ìwé 1-32
Ẹ́sírà àtàwọn ọmọ Ísírẹ́lì kan wà nínú tẹ́ńpìlì, wọ́n sì ń ṣọ̀fọ̀. Ṣẹkanáyà di ọwọ́ Ẹ́sírà mú kó lè dìde.

Ilé Ìṣọ́ Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

NOVEMBER 2023

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ: JANUARY 8–FEBRUARY 4, 2024

© 2023 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania

Ìtẹ̀jáde yìí kì í ṣe títà. Ó jẹ́ ara iṣẹ́ ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì kárí ayé tá à ń fi ọrẹ àtinúwá tì lẹ́yìn. Tó o bá fẹ́ ṣètọrẹ, jọ̀wọ́ lọ sí ìkànnì donate.jw.org.

Inú Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun la ti mú gbogbo ẹsẹ Bíbélì tá a lò, àfi tá a bá sọ pé Bíbélì míì la lò.

ÀWÒRÁN IWÁJÚ ÌWÉ:

Ẹ́sírà ń sunkún, inú ẹ̀ sì bà jẹ́ bó ṣe ń gbàdúrà nínú tẹ́ńpìlì nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn èèyàn Ọlọ́run. Àwọn èèyàn náà sì ń sunkún. Ṣẹkanáyà tu Ẹ́sírà nínú, ó sì fi dá a lójú pé: “Ìrètí ṣì wà fún Ísírẹ́lì. . . . A sì wà pẹ̀lú rẹ.”—Ẹ́sírà 10:2, 4 (Wo àpilẹ̀kọ fún ìkẹ́kọ̀ọ́ 48, ìpínrọ̀ 17)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́