ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 349
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Àwọn Onídàájọ́

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Àwọn Onídàájọ́
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Agbára Jèhófà Mú Kí Sámúsìnì Borí!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà Bíi Ti Sámúsìn
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2023
  • “Idà Jèhófà Àti Ti Gídíónì!”
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • Ọkùnrin Tó Lágbára Jù Lọ
    Ìwé Ìtàn Bíbélì
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Àwọn Onídàájọ́

ÀWỌN ONÍDÀÁJỌ́

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Àwọn tí Júdà àti Síméónì ṣẹ́gun (1-20)

    • Àwọn ará Jébúsì ò kúrò ní Jerúsálẹ́mù (21)

    • Jósẹ́fù gba Bẹ́tẹ́lì (22-26)

    • Wọn ò lé àwọn ọmọ Kénáánì kúrò tán (27-36)

  • 2

    • Áńgẹ́lì Jèhófà kìlọ̀ fún wọn (1-5)

    • Jóṣúà kú (6-10)

    • Jèhófà yan àwọn onídàájọ́ tó máa gba Ísírẹ́lì sílẹ̀ (11-23)

  • 3

    • Jèhófà dán Ísírẹ́lì wò (1-6)

    • Ótíníẹ́lì, onídàájọ́ àkọ́kọ́ (7-11)

    • Éhúdù onídàájọ́ pa Ẹ́gílónì, ọba tó sanra (12-30)

    • Ṣámúgárì onídàájọ́ (31)

  • 4

    • Jábínì ọba Kénáánì fìyà jẹ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì (1-3)

    • Dèbórà wòlíì obìnrin àti Bárákì onídàájọ́ (4-16)

    • Jáẹ́lì pa Sísérà olórí ogun (17-24)

  • 5

    • Dèbórà àti Bárákì kọrin ìṣẹ́gun (1-31)

      • Àwọn ìràwọ̀ bá Sísérà jà (20)

      • Ọ̀gbàrá Kíṣónì kún àkúnya (21)

      • Àwọn tó nífẹ̀ẹ́ Jèhófà dà bí oòrùn (31)

  • 6

    • Mídíánì fìyà jẹ Ísírẹ́lì (1-10)

    • Áńgẹ́lì kan fi dá Gídíónì Onídàájọ́ lójú pé Jèhófà máa ràn án lọ́wọ́ (11-24)

    • Gídíónì wó pẹpẹ Báálì lulẹ̀ (25-32)

    • Ẹ̀mí Ọlọ́run bà lé Gídíónì (33-35)

    • Ó fi ìṣùpọ̀ irun àgùntàn wádìí ọ̀rọ̀ (36-40)

  • 7

    • Gídíónì àti 300 ọkùnrin rẹ̀ (1-8)

    • Àwọn ọmọ ogun Gídíónì ṣẹ́gun Mídíánì (9-25)

      • “Idà Jèhófà àti ti Gídíónì!” (20)

      • Ibùdó Mídíánì dà rú (21, 22)

  • 8

    • Àwọn èèyàn Éfúrémù bínú sí Gídíónì (1-3)

    • Wọ́n lé àwọn ọba Mídíánì mú, wọ́n sì pa wọ́n (4-21)

    • Gídíónì ò gbà kí wọ́n fi òun jọba (22-27)

    • Àkópọ̀ ìtàn ìgbésí ayé Gídíónì (28-35)

  • 9

    • Ábímélékì jọba ní Ṣékémù (1-6)

    • Jótámù ṣe àkàwé (7-21)

    • Ìjọba Ábímélékì ni àwọn èèyàn lára (22-33)

    • Ábímélékì gbógun ja Ṣékémù (34-49)

    • Obìnrin kan ṣe Ábímélékì léṣe, ó sì kú (50-57)

  • 10

    • Tólà àti Jáírì onídàájọ́ (1-5)

    • Ísírẹ́lì ṣọ̀tẹ̀, ó sì ronú pìwà dà (6-16)

    • Àwọn ọmọ Ámónì halẹ̀ mọ́ Ísírẹ́lì (17, 18)

  • 11

    • Wọ́n lé Jẹ́fútà onídàájọ́ jáde, àmọ́ wọ́n sọ ọ́ di olórí nígbà tó yá (1-11)

    • Jẹ́fútà bá àwọn ọmọ Ámónì sọ̀rọ̀ (12-28)

    • Ẹ̀jẹ́ tí Jẹ́fútà jẹ́ àti ọmọbìnrin rẹ̀ (29-40)

      • Ọmọbìnrin náà ò lọ́kọ rárá (38-40)

  • 12

    • Wọ́n bá àwọn ọmọ Éfúrémù jà (1-7)

      • Wọ́n ní kí wọ́n pe Ṣíbólẹ́tì (6)

    • Íbísánì, Élónì àti Ábídónì di onídàájọ́ (8-15)

  • 13

    • Áńgẹ́lì kan wá sọ́dọ̀ Mánóà àti ìyàwó rẹ̀ (1-23)

    • Wọ́n bí Sámúsìn (24, 25)

  • 14

    • Sámúsìn onídàájọ́ fẹ́ fi ọmọ Filísínì ṣe aya (1-4)

    • Ẹ̀mí Jèhófà mú kí Sámúsìn pa kìnnìún (5-9)

    • Sámúsìn pa àlọ́ níbi ìgbéyàwó (10-19)

    • Wọ́n fún ọkùnrin míì ní ìyàwó Sámúsìn (20)

  • 15

    • Sámúsìn gbẹ̀san lára àwọn Filísínì (1-20)

  • 16

    • Sámúsìn lọ sí Gásà (1-3)

    • Sámúsìn àti Dẹ̀lílà (4-22)

    • Sámúsìn gbẹ̀san, ó sì kú (23-31)

  • 17

    • Àwọn ère Míkà àti àlùfáà rẹ̀ (1-13)

  • 18

    • Àwọn ọmọ Dánì ń wá ilẹ̀ (1-31)

      • Wọ́n kó àwọn ère Míkà, wọ́n sì mú àlùfáà rẹ̀ (14-20)

      • Wọ́n gba Láíṣì, wọ́n sì yí orúkọ rẹ̀ pa dà sí Dánì (27-29)

      • Wọ́n jọ́sìn ère ní Dánì (30, 31)

  • 19

    • Ìṣekúṣe tí àwọn ọmọ Bẹ́ńjámínì ṣe ní Gíbíà (1-30)

  • 20

    • Wọ́n gbógun ja àwọn ọmọ Bẹ́ńjámínì (1-48)

  • 21

    • Wọ́n gba ẹ̀yà Bẹ́ńjámínì sílẹ̀ (1-25)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́