ÀWỌN ONÍDÀÁJỌ́
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
1
Àwọn tí Júdà àti Síméónì ṣẹ́gun (1-20)
Àwọn ará Jébúsì ò kúrò ní Jerúsálẹ́mù (21)
Jósẹ́fù gba Bẹ́tẹ́lì (22-26)
Wọn ò lé àwọn ọmọ Kénáánì kúrò tán (27-36)
2
3
Jèhófà dán Ísírẹ́lì wò (1-6)
Ótíníẹ́lì, onídàájọ́ àkọ́kọ́ (7-11)
Éhúdù onídàájọ́ pa Ẹ́gílónì, ọba tó sanra (12-30)
Ṣámúgárì onídàájọ́ (31)
4
Jábínì ọba Kénáánì fìyà jẹ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì (1-3)
Dèbórà wòlíì obìnrin àti Bárákì onídàájọ́ (4-16)
Jáẹ́lì pa Sísérà olórí ogun (17-24)
5
6
Mídíánì fìyà jẹ Ísírẹ́lì (1-10)
Áńgẹ́lì kan fi dá Gídíónì Onídàájọ́ lójú pé Jèhófà máa ràn án lọ́wọ́ (11-24)
Gídíónì wó pẹpẹ Báálì lulẹ̀ (25-32)
Ẹ̀mí Ọlọ́run bà lé Gídíónì (33-35)
Ó fi ìṣùpọ̀ irun àgùntàn wádìí ọ̀rọ̀ (36-40)
7
8
Àwọn èèyàn Éfúrémù bínú sí Gídíónì (1-3)
Wọ́n lé àwọn ọba Mídíánì mú, wọ́n sì pa wọ́n (4-21)
Gídíónì ò gbà kí wọ́n fi òun jọba (22-27)
Àkópọ̀ ìtàn ìgbésí ayé Gídíónì (28-35)
9
Ábímélékì jọba ní Ṣékémù (1-6)
Jótámù ṣe àkàwé (7-21)
Ìjọba Ábímélékì ni àwọn èèyàn lára (22-33)
Ábímélékì gbógun ja Ṣékémù (34-49)
Obìnrin kan ṣe Ábímélékì léṣe, ó sì kú (50-57)
10
Tólà àti Jáírì onídàájọ́ (1-5)
Ísírẹ́lì ṣọ̀tẹ̀, ó sì ronú pìwà dà (6-16)
Àwọn ọmọ Ámónì halẹ̀ mọ́ Ísírẹ́lì (17, 18)
11
Wọ́n lé Jẹ́fútà onídàájọ́ jáde, àmọ́ wọ́n sọ ọ́ di olórí nígbà tó yá (1-11)
Jẹ́fútà bá àwọn ọmọ Ámónì sọ̀rọ̀ (12-28)
Ẹ̀jẹ́ tí Jẹ́fútà jẹ́ àti ọmọbìnrin rẹ̀ (29-40)
12
13
14
Sámúsìn onídàájọ́ fẹ́ fi ọmọ Filísínì ṣe aya (1-4)
Ẹ̀mí Jèhófà mú kí Sámúsìn pa kìnnìún (5-9)
Sámúsìn pa àlọ́ níbi ìgbéyàwó (10-19)
Wọ́n fún ọkùnrin míì ní ìyàwó Sámúsìn (20)
15
16
17
18
19
20
21