ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 1200
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Dáníẹ́lì

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Dáníẹ́lì
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Dáníẹ́lì
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2007
  • Máa Fiyè Sí Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run Fún Ọjọ́ Wa
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
  • Ìwé Dáníẹ́lì àti Ìwọ
    Kíyè sí Àsọtẹ́lẹ̀ Dáníẹ́lì
  • Ońṣẹ́ kan Láti Ọ̀dọ̀ Ọlọ́run fún un Lókun
    Kíyè sí Àsọtẹ́lẹ̀ Dáníẹ́lì
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Dáníẹ́lì

DÁNÍẸ́LÌ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Àwọn ará Bábílónì dó ti Jerúsálẹ́mù (1, 2)

    • Wọ́n dìídì dá àwọn ọmọ ọba tí wọ́n kó lẹ́rú lẹ́kọ̀ọ́ (3-5)

    • Wọ́n dán ìṣòtítọ́ àwọn Hébérù mẹ́rin wò (6-21)

  • 2

    • Ọba Nebukadinésárì lá àlá tó bà á lẹ́rù (1-4)

    • Amòye kankan ò lè rọ́ àlá náà (5-13)

    • Dáníẹ́lì ní kí Ọlọ́run ran òun lọ́wọ́ (14-18)

    • Dáníẹ́lì yin Ọlọ́run torí pé Ó ṣí àṣírí náà payá (19-23)

    • Dáníẹ́lì rọ́ àlá náà fún ọba (24-35)

    • Ìtumọ̀ àlá náà (36-45)

      • Òkúta tó ṣàpẹẹrẹ ìjọba máa fọ́ ère náà túútúú (44, 45)

    • Ọba dá Dáníẹ́lì lọ́lá (46-49)

  • 3

    • Ère wúrà tí Ọba Nebukadinésárì ṣe (1-7)

      • Ó ní kí wọ́n jọ́sìn ère náà (4-6)

    • Wọ́n fẹ̀sùn kan àwọn Hébérù mẹ́ta pé wọn ò ṣègbọràn (8-18)

      • “A ò ní sin àwọn ọlọ́run rẹ” (18)

    • Wọ́n jù wọ́n sínú iná ìléru (19-23)

    • Ọlọ́run gbà wọ́n sílẹ̀ nínú iná náà lọ́nà ìyanu (24-27)

    • Ọba gbé Ọlọ́run àwọn Hébérù ga (28-30)

  • 4

    • Ọba Nebukadinésárì gbà pé Ọlọ́run ni ọba (1-3)

    • Ọba lá àlá nípa igi kan (4-18)

      • Ìgbà méje kọjá lórí igi tí wọ́n gé (16)

      • Ọlọ́run ni Alákòóso aráyé (17)

    • Dáníẹ́lì túmọ̀ àlá náà (19-27)

    • Ó kọ́kọ́ ṣẹ sí ọba lára (28-36)

      • Orí ọba dà rú fún ìgbà méje (32, 33)

    • Ọba gbé Ọlọ́run ọ̀run ga (37)

  • 5

    • Àsè Ọba Bẹliṣásárì (1-4)

    • Ìkọ̀wé lára ògiri (5-12)

    • Wọ́n ní kí Dáníẹ́lì sọ ìtumọ̀ ọ̀rọ̀ náà (13-25)

    • Ìtumọ̀: Bábílónì máa ṣubú (26-31)

  • 6

    • Àwọn ìjòyè ilẹ̀ Páṣíà gbìmọ̀ pọ̀ láti mú Dáníẹ́lì (1-9)

    • Dáníẹ́lì ò yéé gbàdúrà (10-15)

    • Wọ́n ju Dáníẹ́lì sínú ihò kìnnìún (16-24)

    • Ọba Dáríúsì bọlá fún Ọlọ́run Dáníẹ́lì (25-28)

  • 7

    • Ìran àwọn ẹranko mẹ́rin (1-8)

      • Ìwo kékeré kan tó ń gbéra ga jáde (8)

    • Ẹni Ọjọ́ Àtayébáyé mú ìjókòó ní kọ́ọ̀tù (9-14)

      • Wọ́n fi ọmọ èèyàn ṣe ọba (13, 14)

    • A fi ìtumọ̀ han Dáníẹ́lì (15-28)

      • Ọba mẹ́rin ni àwọn ẹranko mẹ́rin náà (17)

      • Àwọn ẹni mímọ́ máa gba ìjọba (18)

      • Ìwo mẹ́wàá, tàbí ọba mẹ́wàá, máa dìde (24)

  • 8

    • Ìran àgbò àti òbúkọ (1-14)

      • Ìwo kékeré kan gbé ara rẹ̀ ga (9-12)

      • Títí di 2,300 alẹ́ àti àárọ̀ (14)

    • Gébúrẹ́lì túmọ̀ ìran náà (15-27)

      • Àlàyé nípa àgbò àti òbúkọ náà (20, 21)

      • Ọba kan tí ojú rẹ̀ le dìde (23-25)

  • 9

    • Dáníẹ́lì gbàdúrà ìjẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ (1-19)

      • Jerúsálẹ́mù máa dahoro fún 70 ọdún (2)

    • Gébúrẹ́lì wá bá Dáníẹ́lì (20-23)

    • Àsọtẹ́lẹ̀ nípa àádọ́rin ọ̀sẹ̀ (24-27)

      • Mèsáyà máa fara hàn lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ 69 (25)

      • Wọ́n máa pa Mèsáyà (26)

      • Ìlú náà àti ibi mímọ́ máa pa run (26)

  • 10

    • Ìránṣẹ́ Ọlọ́run bẹ Dáníẹ́lì wò (1-21)

      • Máíkẹ́lì ran áńgẹ́lì náà lọ́wọ́ (13)

  • 11

    • Àwọn ọba Páṣíà àti Gíríìsì (1-4)

    • Àwọn ọba gúúsù àti àríwá (5-45)

      • Afipámúni máa dìde (20)

      • A ṣẹ́ Aṣáájú májẹ̀mú náà (22)

      • Ó yin ọlọ́run ibi ààbò lógo (38)

      • Ọba gúúsù àti ọba àríwá máa kọ lu ara wọn (40)

      • Ìròyìn tó ń yọni lẹ́nu láti ìlà oòrùn àti àríwá (44)

  • 12

    • “Àkókò òpin” àti ohun tó máa ṣẹlẹ̀ lẹ́yìn náà (1-13)

      • Máíkẹ́lì máa dìde (1)

      • Àwọn tó ní ìjìnlẹ̀ òye máa tàn yinrin (3)

      • Ìmọ̀ tòótọ́ máa pọ̀ yanturu (4)

      • Dáníẹ́lì máa dìde fún ìpín rẹ̀ (13)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́