ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sjj orin 48
  • Máa Bá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Máa Bá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́
  • “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Bíbá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́
    Kọrin sí Jèhófà
  • Bá Ọlọ́run Rìn!
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Ṣé Wàá Bá Ọlọ́run Rìn?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • Bíbá Ọlọ́run Rìn—Àwọn Ìgbésẹ̀ Àkọ́kọ́
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
Àwọn Míì
“Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
sjj orin 48

ORIN 48

Máa Bá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́

Bíi Ti Orí Ìwé

(Míkà 6:8)

  1. 1. Ní ojoojúmọ́ ayé wa,

    A ó máa fìrẹ̀lẹ̀ b’Ọ́lọ́run rìn.

    Inú rere àìlẹ́tọ̀ọ́sí

    Ló fún àwọn tó fẹ́ dọ̀rẹ́ rẹ̀.

    Ìfẹ́ ló mú kó fún wa ní

    Àǹfààní láti bá a rìn.

    Bá a ṣe yara wa sí mímọ́,

    Ká má fi Jèhófà sílẹ̀.

  2. 2. Lákòókò t’Èṣù ń bínú yìí,

    Tí òpin sì ń yára sún mọ́lé,

    À ń kojú inúnibíni

    Tó lè fẹ́ mú ká juwọ́ sílẹ̀.

    Àmọ́ Jáà máa ń dáàbò bò wá;

    Ká má kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀.

    Ká fi gbogbo ọkàn wa sìn ín,

    Ká jẹ́ adúróṣinṣin sí i.

  3. 3. Jèhófà máa ń fi Ọ̀rọ̀ rẹ̀

    Àti ẹ̀mí rẹ̀ ràn wá lọ́wọ́.

    Ó máa ń lo ìjọ Kristẹni,

    Ó sì tún máa ń gbọ́ àdúrà wa.

    Bí a ṣe ń bá Jèhófà rìn,

    Yóò mú ká ṣohun tó tọ́.

    Yóò mú ká lè dúró ṣinṣin,

    Ká sì máa fìrẹ̀lẹ̀ bá a rìn.

(Tún wo Jẹ́n. 5:24; 6:9; 1 Ọba 2:​3, 4.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́