ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb22 September ojú ìwé 15
  • Ohun Tó Lè Tù Wá Nínú Kí Àjíǹde Tó Dé

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Lè Tù Wá Nínú Kí Àjíǹde Tó Dé
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Tí Ẹni Tó O Fẹ́ràn Bá Kú
    Àkójọ Àpilẹ̀kọ àti Fídíò
  • Ẹ̀kọ́ Àjíǹde Kàn Ọ́
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • Ṣé Aṣọ Ìsìnkú Turin Ni Wọ́n Fi Sin Òkú Jésù?
    Ohun Tí Bíbélì Sọ
  • Báwo Ni Ìgbàgbọ́ Nínú Àjíǹde Ṣe Jinlẹ̀ Tó Lọ́kàn Rẹ?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
mwb22 September ojú ìwé 15
Inú ìyá kan dùn bó ṣe rí ọmọbìnrin ẹ̀ tó jíǹde nínú Párádísè.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

Ohun Tó Lè Tù Wá Nínú Kí Àjíǹde Tó Dé

Tí ẹni tá a fẹ́ràn bá kú, ìrètí tá a ní pé ẹni náà máa jí dìde máa ń tù wá nínú. Síbẹ̀ náà, ẹ̀ṣẹ̀ àti ikú máa ń kó ẹ̀dùn ọkàn bá gbogbo wa. (Ais 25:7, 8) Ìdí kan rèé tó fi jẹ́ pé “gbogbo ìṣẹ̀dá jọ ń kérora nìṣó, wọ́n sì jọ wà nínú ìrora.” (Ro 8:22) Kí àjíǹde tó wáyé, kí ló lè tù wá nínú ní báyìí téèyàn wa bá kú? A máa rí àwọn ìlànà tó lè ràn wá lọ́wọ́ nínú Bíbélì Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.

Ẹ WO FÍDÍÒ NÁÀ TÍ ẸNI TÓ O FẸ́RÀN BÁ KÚ, KẸ́ Ẹ SÌ DÁHÙN ÀWỌN ÌBÉÈRÈ YÌÍ:

  • Kí ló kó ẹ̀dùn ọkàn bá Danielle, Masahiro àti Yoshimi?

  • Àwọn àbá márùn-ún wo la mẹ́nu kan nínú fídíò yìí, báwo ló sì ṣe ràn wọ́n lọ́wọ́?

  • Ta ni Orísun gbogbo ìtùnú?—2Kọ 1:3, 4

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́