ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • ijwfq àpilẹ̀kọ 5
  • Kí Nìdí Tí Ẹ Fi Ń Jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Kí Nìdí Tí Ẹ Fi Ń Jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà?
  • Àwọn Ìbéèrè Táwọn Èèyàn Sábà Máa Ń Béèrè Nípa Ẹlẹ́rìí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Kí Nìdí Tí Wọ́n Fi Ń Pè Wá Ní Ẹlẹ́rìí Jèhófà?
    Àwọn Wo Ló Ń Ṣe Ìfẹ́ Jèhófà Lóde Òní?
  • Idi Tí A Fi Gbọdọ Mọ Orukọ Ọlọrun
    Orukọ Atọrunwa naa Tí Yoo Wà Titilae
  • Jèhófà Gbé Orúkọ Rẹ̀ Lékè
    Ìjọba Ọlọ́run Ti Ń Ṣàkóso!
  • Máa Gbé Orúkọ Ńlá Jèhófà Ga
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
Àwọn Míì
Àwọn Ìbéèrè Táwọn Èèyàn Sábà Máa Ń Béèrè Nípa Ẹlẹ́rìí Jèhófà
ijwfq àpilẹ̀kọ 5
Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń wàásù

Kí Nìdí Tí Ẹ Fi Ń Jẹ́ Ẹlẹ́rìí Jèhófà?

Jèhófà ni orúkọ Ọlọ́run bó ṣe wà nínú Bíbélì. (Ẹ́kísódù 6:3; Sáàmù 83:18) Ẹlẹ́rìí ni ẹni tó ń sọ ohun tó dá a lójú tàbí òtítọ́ tó mọ̀ dájú. Nítorí náà, orúkọ wa, Ẹlẹ́rìí Jèhófà, fi hàn pé a jẹ́ àwùjọ Kristẹni tó ń sọ òtítọ́ nípa Jèhófà, Ẹlẹ́dàá ohun gbogbo. (Ìṣípayá 4:11) À ń jẹ́rìí fún àwọn èèyàn nípasẹ̀ ọ̀nà tí à ń gbà gbé ìgbésí ayé wa àti nípa sísọ ohun tá a kọ́ nínú Bíbélì fún wọn.—Aísáyà 43:10-12; 1 Pétérù 2:12

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́