ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • ijwbq àpilẹ̀kọ 48
  • Ṣé Ọlọ́run Ló Dá Èṣù?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ṣé Ọlọ́run Ló Dá Èṣù?
  • Ohun Tí Bíbélì Sọ
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun tí Bíbélì sọ
  • Ṣé Ọlọ́run Ló Dá Èṣù?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
  • Ohun tí Bíbélì sọ
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
  • Èṣù Kì Í Ṣe Ẹni Ìtàn Àròsọ
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2001
  • Ta Ló Ń Ṣàkóso Ayé Yìí?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
Àwọn Míì
Ohun Tí Bíbélì Sọ
ijwbq àpilẹ̀kọ 48
Ańgẹ́lì tó ṣàìgbọràn tó sì di Èṣù

Ṣé Ọlọ́run Ló Dá Èṣù?

Ohun tí Bíbélì sọ

Bíbélì sọ pé Ọlọ́run kọ́ ló dá Èṣù. Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹni tí Ọlọ́run dá ló di Èṣù. Bíbélì sọ nípa Ọlọ́run pé: “Pípé ni ìgbòkègbodò rẹ̀, nítorí gbogbo ọ̀nà rẹ̀ jẹ́ ìdájọ́ òdodo. Ọlọ́run ìṣòtítọ́, ẹni tí kò sí àìṣèdájọ́ òdodo lọ́dọ̀ rẹ̀; Olódodo àti adúróṣánṣán ni.” (Diutarónómì 32:3-5) Látinú ọ̀rọ̀ yìí, a lè rí i pé Sátánì Èṣù jẹ́ ẹni pípé àti olódodo nígbà kan rí, ìyẹn ọ̀kan lára àwọn áńgẹ́lì tó jẹ́ ọmọ Ọlọ́run.

Ní Jòhánù 8:44, Jésù sọ pé Èṣù ‘kò dúró ṣinṣin nínú òtítọ́,’ tó túmọ̀ sí pé Sátánì ti fìgbà kan rí jẹ́ olóòótọ́ àti aláìlẹ́gàn.

Àmọ́, bíi ti ìyókù àwọn áńgẹ́lì Jèhófà tí wọ́n jẹ́ ọlọ́gbọ́n, áńgẹ́lì tó di Sátánì ní òmìnira láti yan ohun tó dára tàbí ohun tí kò dára. Nígbà tó yàn láti máa tako Ọlọ́run tó sì mú kí tọkọtaya àkọ́kọ́ dara pọ̀ mọ́ òun, ó sọ ara rẹ̀ di Sátánì, tó túmọ̀ sí “Alátakò”—Jẹ́nẹ́sísì 3:1-5; Ìṣípayá 12:9.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́