Àfikún Àlàyé
^ [1] (ìpínrọ̀ 4) Ó ṣeé ṣe kó jẹ́ pé ọjọ́ kan náà tí Jèhófà fún Mósè ní ìwé Òfin lórí òkè Sínáì ni Àjọyọ̀ Pẹ́ńtíkọ́sì bọ́ sí. (Ẹ́kísódù 19:1) Torí náà, ó ṣeé ṣe kí ọjọ́ tí Mósè mú orílẹ̀-èdè Ísírẹ́lì wọnú májẹ̀mú Òfin bọ́ sí ọjọ́ kan náà pẹ̀lú ọjọ́ tí Jésù mú àwọn ẹni àmì òróró wọnú májẹ̀mú tuntun.