Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
d Òfin Mósè sọ pé ọkùnrin tó bá bá wúńdíá kan sùn ní láti fẹ́ ẹ. (Diutarónómì 22:28, 29) Bí ó ti wù kó rí, ìyẹn ò sọ ìgbéyàwó di dandan, nítorí bàbá ọmọdébìnrin náà lè má fara mọ́ ọn. (Ẹ́kísódù 22:16, 17) Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn Kristẹni lónìí kò sí lábẹ́ Òfin yẹn mọ́, èyí tẹnu mọ́ bí ẹ̀ṣẹ̀ ìbálòpọ̀ láìṣègbéyàwó ṣe wúwo tó.—Wo “Ìbéèrè Láti Ọwọ́ Àwọn Òǹkàwé” nínú Ilé Ìṣọ́, November 15, 1989.