Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ní àwọn alàgbà ìjọ tí wọ́n lè lọ bá. Bó tiẹ̀ jẹ́ pé kì í ṣe iṣẹ́ wọn ní láti máa tojú bọ ọ̀rọ̀ àwọn lọ́kọláya tí kì í ṣe ọ̀rọ̀ tó kàn wọ́n, àwọn alàgbà lè ṣe ìrànwọ́ lọ́nà tí ń tuni lára fún àwọn tọkọtaya tí wọ́n ní ìṣòro.—Jákọ́bù 5:14, 15.