ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

a Bíbélì sọ nípa “Ha-Mágẹ́dọ́nì,” èyí tá a tún mọ̀ sí “ogun ọjọ́ ńlá Ọlọ́run Olódùmarè.” Kì í ṣe ogun tí ẹ̀dá èèyàn ń jà ni èyí tọ́ka sí o, àmọ́ ó ń tọ́ka sí bí Ọlọ́run ṣe máa ṣa àwọn èèyàn búburú sọ́tọ̀ tá á sì pa wọ́n run. Nítorí náà, èèyàn ò lè fi ti Ha-Mágẹ́dọ́nì kẹ́wọ́ pé òun ló mú kí ogun tí wọ́n ń jà lóde òní tọ̀nà tàbí kéèyàn máa rò pé Ọlọ́run fọwọ́ sí àwọn ogun náà.—Ìṣípayá 16:14, 16; 21:8.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́