Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Àwọn àlùfáà burúkú kan tiẹ̀ sọ pé inú Ọlọ́run dùn sí bí wọ́n ṣe ń ta ọmọ èèyàn, tí wọ́n ń hùwà ìkà sí wọn. Látàrí èyí, ọ̀pọ̀ èèyàn ṣì ń ronú lọ́nà òdì pé Bíbélì dá irú ìwà ìkà bẹ́ẹ̀ láre. Irọ́ gbuu lèyí, Bíbélì kò tì í lẹ́yìn rárá. Jọ̀wọ́ wo àpilẹ̀kọ náà, “Ojú Ìwòye Bíbélì: Ǹjẹ́ Ọlọ́run Fara Mọ́ Ṣíṣe Òwò Ẹrú?,” nínú ìtẹ̀jáde Jí! September 8, 2001.