Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ní ṣáńgílítí, ó túmọ̀ sí, “tí Ọlọ́run kà sí ẹni rírẹwà.” Gẹ́gẹ́ bí ìwé The Expositor’s Bible Commentary ṣe sọ, ó lè ṣàìjẹ́ pé ẹwà àbímọ́ni tí ọmọ náà ní nìkan ni gbólóhùn náà ń sọ nípa rẹ̀, bí kò ṣe “àwọn ànímọ́ ti inú ọkàn rẹ̀” lọ́hùn-ún.