Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Kódà, bí òfin orílẹ̀-èdè táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń gbé bá ta ko ẹ̀rí ọkàn wọn tí wọ́n ti fi Bíbélì kọ́, wọn kì í lọ́wọ́ nínú fífi ẹ̀hónú hàn, wọn kì í sì í báwọn olóṣèlú yíde kiri lọ́nà èyíkéyìí nítorí àtiyí irú òfin bẹ́ẹ̀ padà.
a Kódà, bí òfin orílẹ̀-èdè táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń gbé bá ta ko ẹ̀rí ọkàn wọn tí wọ́n ti fi Bíbélì kọ́, wọn kì í lọ́wọ́ nínú fífi ẹ̀hónú hàn, wọn kì í sì í báwọn olóṣèlú yíde kiri lọ́nà èyíkéyìí nítorí àtiyí irú òfin bẹ́ẹ̀ padà.