Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Léfítíkù 19:28 sọ pé: “Ẹ kò sì gbọ́dọ̀ kọ ara yín lábẹ nítorí ọkàn tí ó ti di olóògbé.” Àṣà àwọn kèfèrí yìí, tí wọ́n fi máa ń bọ àwọn ọlọ́run wọn tí wọn gbà gbọ́ pé ó máa ń bójú tó àwọn òkú, yàtọ̀ pátápátá sí àṣà dídọ́gbẹ́ síra ẹni lára tá à ń jíròrò yìí o.