Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
e Àwọn àpilẹ̀kọ tó dá lórí àwọn ohun tó máa ń fa dídọ́gbẹ́ síra ẹni lára wà nínú àwọn Jí! tá a ti tẹ̀ nígbà kan. Bí àpẹẹrẹ, wo ọ̀wọ́ àpilẹ̀kọ náà, “Lílóye Àwọn Tí Ìṣesí Wọn Ṣàdédé Ń Yí Padà” (January 8, 2004), “Ìrànwọ́ fún Àwọn Èwe Tó Sorí Kọ́” (September 8, 2001), àti èyí tó sọ̀rọ̀ nípa ohun tó ń fa ìṣòro àìjẹun dáadáa tó wà nínú Jí! January 22, 1999, lédè Gẹ̀ẹ́sì, tó fi mọ́ àpilẹ̀kọ náà “Àwọn Ọ̀dọ́ Béèrè Pé . . . Obi Onimukumu-ọti kan—Bawo Ni Mo Ṣe Lè Koju Rẹ̀?” (August 8, 1992).