Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Nínú Bíbélì, “ọkàn” túmọ̀ sí odidi èèyàn kan, kì í ṣe ohun kan tó dá wà nínú ara. Jẹ́nẹ́sísì 2:7 sọ pé: “Jèhófà Ọlọ́run sì bẹ̀rẹ̀ sí ṣẹ̀dá ọkùnrin náà láti inú ekuru ilẹ̀, ó sì fẹ́ èémí ìyè sínú ihò imú rẹ̀, ọkùnrin náà sì wá di alààyè ọkàn.” Ọlọ́run kò fún Ádámù ní ọkàn tó ń gbé nínú ara rẹ̀. Kàkà bẹ́ẹ̀, Ádámù fúnra rẹ̀ ni alààyè ọkàn.