Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
c Gbólóhùn náà “ìbàlágà” kò sí nínú Bíbélì. Ó ṣe kedere pé àtìgbà ọmọdé ni àwọn ọ̀dọ́ tó wà láàárín àwọn èèyàn Ọlọrun ti máa ń bá àwọn àgbàlagbà da nǹkan pọ̀, kí ẹ̀sìn Kristẹni tó dé àti lẹ́yìn tó dé. Èyí kò sì rí bẹ́ẹ̀ nínú ọ̀pọ̀ àṣà ìbílẹ̀ lóde òní.