Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Nínú ọ̀pọ̀ Bíbélì, wọ́n ti yọ orúkọ Ọlọ́run kúrò, wọ́n sì fi “OLÚWA” èyí tí wọ́n kọ ní lẹ́tà gàdàgbà, rọ́pò rẹ̀. Nínú àwọn Bíbélì míì, ìwọ̀nba àwọn ẹsẹ mélòó kan àti àlàyé ìsàlẹ̀ ìwé ni wọ́n kọ orúkọ náà sí. Àmọ́ orúkọ náà fara hàn lọ́pọ̀ ìgbà nínú Bíbélì Ìwé Mímọ́ ní Ìtumọ̀ Ayé Tuntun.