Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Ayafi bi a bá tọkafihan pe òmíràn ni, awọn ẹsẹ Ìwémímọ́-ìsìn tí a fàyọ ninu itẹjade yii jẹ́ lati inu itumọ Bibeli ti ede Yoruba. Nibi tí a bá ti fi NW hàn tẹle ẹsẹ-iwemimọ-ìsìn kan tí a fàyọ, ó fihan pe a ti tumọ ẹsẹ naa lati inu Bibeli ede Gẹẹsi ti New World Translation of the Holy Scriptures, itẹjade titun ti 1984.