Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Àmọ́ o, kíyè sí i pé Ìṣípayá 12:9 sọ̀rọ̀ nípa “dírágónì ńlá náà . . . [àti] àwọn áńgẹ́lì rẹ̀.” Nítorí náà, kì í ṣe kìkì pé Èṣù sọ ara rẹ̀ di ayédèrú ọlọ́run nìkan ni ṣùgbọ́n ó tún gbìyànjú láti di olú-áńgẹ́lì, bó tilẹ̀ jẹ́ pé Bíbélì ò fìgbà kankan fún un lórúkọ oyè yẹn.