Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Bíbélì lo ọ̀rọ̀ náà, “ìtẹ́” lọ́nà tó jọ èyí nínú àwọn ọ̀rọ̀ tí onísáàmù kan sọ nípa Jésù nínú àsọtẹ́lẹ̀, tó sọ pé: “Ọlọ́run ni ìtẹ́ rẹ fún àkókò tí ó lọ kánrin, àní títí láé.” (Sáàmù 45:6) Jèhófà ni orísun, tàbí ìpìlẹ̀, agbára ìṣàkóso Jésù.