c Kíyè sí i pé ọ̀rọ̀ náà, “àwọn orílẹ̀-èdè” sábà máa ń tọ́ka sí àwọn tí kì í ṣe ara Ísírẹ́lì tẹ̀mí. (Ìṣípayá 7:9; 15:4; 20:3; 21:24, 26) Bí Ìwé Mímọ́ ṣe lo ọ̀rọ̀ náà níbí kò túmọ̀ sí pé aráyé á tún ṣì wà nínú àwùjọ orílẹ̀-èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ nígbà Ẹgbẹ̀rúndún Ìṣàkóso náà.