ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

a Fún àpẹẹrẹ, àwọn Yorùbá ní Nigeria ní ìgbàgbọ́ àtọwọ́dọ́wọ́ nínú àtúnwáyé ọkàn. Nítorí náà nígbà tí ìyá kan bá ṣòfò ọmọ, yóò ní ẹ̀dùn-ọkàn jíjinlẹ̀ ṣùgbọ́n kìkì fún sáà kúkúrú kan, nítorí gẹ́gẹ́ bí ègbè-orin Yorùbá kan ti wí: “Omi ló dànù. Agbè kò fọ́.” Gẹ́gẹ́ bí ìgbàgbọ́ àwọn Yoruba, èyí túmọ̀sí pé agbè tí ó gba omi ró, ìyá náà, lè bí ọmọ mìíràn​—bóyá àtúnwáyé ẹni náà tí ó kú. Àwọn Ẹlẹ́rìí Jehofa kìí tẹ̀lé àṣà àtọwọ́dọ́wọ́ èyíkéyìí tí a gbékarí ìgbàgbọ́ nínú ohun asán tí ó wá láti inú èrò èké nípa àìlèkú ọkàn àti àtúnwáyé, èyí tí kò ní ìpìlẹ̀ nínú Bibeli.​—Oniwasu 9:​5, 10; Esekieli 18:​4, 20.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́