Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ọ̀rọ̀ Hébérù náà, da·vaqʹ, tí a túmọ̀ sí “fà mọ́” níhìn-ín, “ní òye ti dídìrọ̀mọ́ ẹnì kan láti inú ìfẹ́ni àti ìdúróṣinṣin.”4 Ní èdè Gírí ìkì, ọ̀rọ̀ tí a túmọ̀ sí “yóò fà mọ́” nínú Mátíù 19:5 ní ìbátan pẹ̀lú ọ̀rọ̀ tí ó túmọ̀ sí “láti lẹ̀ pọ̀” “láti rẹ́ pọ̀,” “láti so pọ̀ dan-indan-in.”5