Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Ní àwọn àkókò tí a kọ Bíbélì, ọ̀rọ̀ náà “ọ̀pá” (sheʹvet lédè Hébérù) túmọ̀ sí “igi” tàbí “ọ̀pá gbọọrọ,” irú èyí tí àwọn olùṣọ́ àgùntàn máa ń lò.10 Nínú àyíká ọ̀rọ̀ yí, ọ̀pá àṣẹ dámọ̀ràn ìtọ́sọ́nà onífẹ̀ẹ́, kì í ṣe ìwà òkú òǹrorò.—Fí wé Sáàmù 23:4.