Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
d Ìwé ìròyìn Biblical Archaeology Review sọ pé: “Àwọn ògbógi Bábílónì kọ ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn àpẹẹrẹ abàmì sílẹ̀ lẹ́sẹẹsẹ. . . . Nígbà tí Bẹliṣásárì sọ pé dandan ni kí òun mọ ohun tí ìkọ̀wé ara ògiri náà jẹ́, ó dájú pé àwọn amòye Bábílónì wọ̀nyí yóò yíjú sí àwọn ìwé atúmọ̀ àwọn àmì wọ̀nyí. Ṣùgbọ́n òfo ni wọ́n já sí.”