Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
b Jésù ṣì ń bá a lọ láti bójú tó iṣẹ́ sísọni di ọmọ ẹ̀yìn yìí. (Ìṣípayá 14:14-16) Lóde òní, Jésù ni àwọn Kristẹni lọ́kùnrin lóbìnrin kà sí Orí ìjọ. (1 Kọ́ríńtì 11:3) Bí ó bá sì tó àkókò lójú Ọlọ́run, Jésù yóò ṣe ojúṣe “aṣáájú àti aláṣẹ” ní ọ̀nà mìíràn, nígbà tó bá dojú ogun àjàṣẹ́gun kọ àwọn ọ̀tá Ọlọ́run nígbà ogun Amágẹ́dọ́nì.—Ìṣípayá 19:19-21.