Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé
a Ọ̀rọ̀ náà “ìwẹ̀fà” tún di èyí tí a ń lò fún ẹni tó jẹ́ òṣìṣẹ́ láàfin láìjẹ́ pé wọ́n tẹ̀ ẹ́ lọ́dàá. Nígbà tó sì ti jọ pé aláwọ̀ṣe ni ará Etiópíà tí Fílípì rì bọmi, tí wọ́n sì tún rì í bọmi ṣáájú kí ọ̀nà tó ṣí sílẹ̀ fún àwọn tí kì í ṣe Júù, a jẹ́ pé irú ìwẹ̀fà bí èyí ni tirẹ̀.—Ìṣe 8:27-39.