ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ

Àlàyé Ìsàlẹ̀ Ìwé

d A tún lè bẹ̀rẹ̀ ẹsẹ yìí báyìí pé: “Ó sì bẹ̀rẹ̀ sí rántí.” (Aísáyà 63:11, àlàyé etí ìwé, NW) Ṣùgbọ́n, èyí kò fi dandan túmọ̀ sí pé Jèhófà ni ẹni tó ń rántí nǹkan wọ̀nyẹn. Bí nǹkan ṣe rí lára àwọn èèyàn Ọlọ́run fúnra wọn ni ọ̀rọ̀ tó tẹ̀ lé e ń sọ, kì í ṣe bí ó ṣe rí lára Jèhófà fúnra rẹ̀. Ìyẹn ni ìwé Soncino Books of the Bible fi túmọ̀ ọ̀rọ̀ yẹn báyìí pé: “Ìyẹn làwọn èèyàn Rẹ̀ fi wá rántí àwọn ọjọ́ pípẹ́ sẹ́yìn.”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́